Home / Àṣà Oòduà / Covid-19 ló sàkóbá fún isé̩ e̩gbè̩rùn kan, ìjo̩ba ìbíle̩ kan – Festus Keyamu

Covid-19 ló sàkóbá fún isé̩ e̩gbè̩rùn kan, ìjo̩ba ìbíle̩ kan – Festus Keyamu

Covid-19 ló sàkóbá fún isé̩ e̩gbè̩rùn kan, ìjo̩ba ìbíle̩ kan – Festus Keyamu
Yínká Àlàbí

Agbejoro agba to n ja fun eto omoniyan to tun je minisita eto ise fun ipinle, Festus Keyamu lo n salaye fun awon oniroyin nipa aseyori Buhari.

Keyamu ni “oro kanle kan baale, yoo kan jeje ni mo jokoo mi”. O ni akoba kekere ko ni ajakale arun coronavirus se fun orileede yii.


O ni ibi ti ijoba kankan ko ronu de ni ijoba Buhari ronu de fun odun merin eleekeji yii. O ni eto ise egberun eniyan ni ijoba ibile kookan ni orileede yii. A si ni ijoba egberin din merindinlogbon (774).

Keyamu ni ijoba si ti seto egberun lona ogun naira fun enikookan losu. O ni eto yii si maa mu banki merin dani, o ni ajosepo awon banki yii lo maa din inawo naa ku.

O ni awon eniyan yii kan maa lo foruko sile ni awon ile ifowo-pamo-si yii. Nomba idanimo (BVN) won ni won fi maa san owo fun won. Eyi ko si tun ni fi aaye ki eniyan kan gbowo eniyan meji dani.


Minisita yii ni ibanuje gidi lo je bi ajakale arun yii se wolu ti ko je ki gbogbo agbaye mo “odo ti won maa da orunla si”.

O ni ju gbogbo re lo, ijoba apapo ko ti da eto gidi naa nu. O ni eto naa si n mumu laya ijoba apapo ti o si maa bere laipe.

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...