Home / Àṣà Oòduà / Fayose kò mo̩ bò̩ò̩lì àti àgbàdo je̩ tó mi,àmó̩… – Fayemi

Fayose kò mo̩ bò̩ò̩lì àti àgbàdo je̩ tó mi,àmó̩… – Fayemi

Gomina ipinle Ekiti, Dr Kayode Fayemi lo n salaye yii nibi eto ori telifison Kan ti arabinrin Morayo Afolabi n dari re.

Leyin ti gomina dahun orisiirisii ibeere ni arabinrin naa wa tun beere asepo to wa laarin oun ati gomina ana ni ipinle naa, Alagba Ayodele Fayose.
Fayemi ni asepo to dan moran wa laarin awon. O ni koda awon pade ni ode kan ti Ojogbon Afe Babalola ti lo gba ebun laipe.

O ni awon si soro daadaa, koda awon tun da apara.
Fayemi ni ko si ija tabi ita laarin awon. Ibe naa ni gomina Fayemi tun ti dahun ibeere iyato to wa laarin awon ti kii se eebu. O ni Olorun lo da onikaluku ni otooto.

O ni gbogbo nnkan daadaa ti Fayose n je ni oun naa le je, o ni koda Fayose gan-an mo pe ko lemii oun nibi agbado ati booli jije. O ni amo oun ko le maa jee laarin oja bii tire.

About ayangalu

x

Check Also

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

A kì í wípé kí ọmọ olówó kó má se yín gan-an gan-anBó bá ṣe yín gan-an gan-an a o ni fètè ìwọ̀fà boA dífá fún Ọ̀rúnmìlà wọ́n ní kí baba kó fi ẹbọ araa rẹ̀ sílẹ̀Wọ́n ní Ẹbọ ayé gbogbo ni kí baba o seỌ̀rúnmìlà ní kí ọmọ Osó kó mà kú oBaba ní k’ọ́mọ Àjẹ́ kó yèNítorí wípé ẹbọ ayé gbogbo ni mo nseIre oo