Home / Àṣà Oòduà / Ìjo̩ba àpapò̩ kéde ‘June 12’ gé̩gé̩ bí o̩jó̩ ìsinmi lé̩nu isé̩

Ìjo̩ba àpapò̩ kéde ‘June 12’ gé̩gé̩ bí o̩jó̩ ìsinmi lé̩nu isé̩

Ìjo̩ba àpapò̩ kéde ‘June 12’ gé̩gé̩ bí o̩jó̩ ìsinmi lé̩nu isé̩

Lati odun to koja ni ijoba apapo ti yi ojo isejoba awa-ara-wa kuro ni ojo kokandinlogbon osu karun-un odun si ojo kejila osu kefa odun.


Eyi waye lati fi se iranti Oloogbe Moshood Kashimaawo Abiola ti gbogbo aye gba pe ibo ojo kejila odun 1994 ni ibo ti o dara ju ni orileede yii.

Won ni ibo naa ni ko ni ojoro ti o si lo ni irowo ati irose ju lati igba ti a ti bere oselu.


“Ko si bi a se le daruko aja ti a ko ni daruko ikoko to a fi see”. Eyi lo mu oro naa kan ijoba ologun igba naa ti Ajagunfehinti Badamosi Babangida je olori. Oun ni o da ibo naa nu bii omi isanwo.


Awon omo Naijiria faraya gidi ni igba naa ki Eledua to ba wa pero sii. Opo emi omo Naijiria lo ba isele naa lo.

Yínká Àlàbí

About AbubakarMuhd

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...