Home / Àṣà Oòduà / Ilé-ẹjọ́ fi mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà fa APC létí

Ilé-ẹjọ́ fi mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà fa APC létí

Ilé-ẹjọ́ fi mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà fa APC létí

Ejo ti ile-ejo giga to fi ikale si ilu Abuja da ni ojo ketala, osu yii ni egbe oselu APC ni awon ko fara mo. Eyi ko tii saba waye ri ni orileede yii, ki ile-ejo giga da ejo ki awon kan wa ni won ni lati tun se ayewo re.


Ejo naa lo fagi le ibo to gbe David Lyon wole gege bi gomina ipinle Bayelsa labe egbe oselu APC. Awon egbe PDP ni won pejo pe iwe eri igbakeji gomina naa ko moyan lori rara. Won ni orisiirisii oruko lo wa lori iwe eri igbakeji gomina naa, iyen Seneto Biobarakuma Degi-Eremienyo.


Ile ejo ni ki awon to ni ejo ko te awon lorun fa asise awon jade sugbon ko si agbejoro to le fa asise Kankan jade ninu ejo naa.
Eyi mu ki ile-ejo giga naa fi milionu mewaa naira fa egbe APC leti. Ile-ejo ni ki won ma se je ki iru re waye mo.

Láti ọwọ́ Yínká Àlàbí

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...