Home / Àṣà Oòduà / Covid-19- kó̩ ló pa Babatunde Oke

Covid-19- kó̩ ló pa Babatunde Oke

Covid-19 ko lo pa Babatunde Oke
Owuro oni ni won kede iku Alaga ijoba ibile Onigbongbo, Ogbeni Babatunde Oke.


Gbogbo iroyin to gbee ni ajakale arun coronavirus lo paa. Won ni baba naa se aisan ranpe ni nnkan bii ose meta seyin sugbon ti ara ti ya.
Won ni alaga yii se odun ileya pelu awon ololufe ati ore pelu ojulumo ni asiko odun naa.

Asiko yii gan-an ni awon olutele oloogbe naa ni ategun tun raaye wo ara re. Won ni bi aisan naa se wo baba naa mole niyen. Eyi mu ki won sare gbee lo si ile iwosan aladaani Kan.


Ile-iwosan naa ni alaga naa ti gbemi mi ti o si je Olorun nipe.
Awon olutele Alaga naa ni won ba IROYIN OWURO soro, won ni covid-19 ko lo pa baba naa. Won ni awon si wa nibi igbokusi ni Yaba lati se oku naa lojo fun igba die.


Awon alaba-sise oloogbe naa ni ti o ba je covid-19 lo pa baba naa, ile-iwosan ko ni fi oku naa sile bee ni won ko si nii gba ki awon toju iru oku naa.

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...