Home / Àṣà Oòduà / Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue

Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue

Ilé-ẹjọ́ tó ga jù ní Samuel Ortom náà ló tún jáwé olúborí ní Benue
Láti ọwọ Yínká Àlàbí


Iroyin yajoyajo to wole bayii lo n jeri sii bi ile ejo to ga ju lo to fi ikale si ilu Abuja se da ejo oludije fun ipo gomina ni ipinle Benue, iyen Emmanuel Jime ti egbe oselu APC nu bi omi isanwo.


Awon adajo meje ti Adajo Olabode Rhodes-vivour je olori fun ni won se idajo naa ni nnkan bii ogbon iseju seyin.
Ile ejo ni gbogbo awijare egbe oselu APC ko lese nile, nipa idi eyi ki gomina Ortom ti egbe oselu PDP si maa se ijoba re lo ni alaafia.


Ti a ko ba gbagbe, ana ode yii naa ni ile ejo yii da ejo awon gomina merin nigba ti ti ipinle Imo waye ni ose to koja bi o tile je pe iwode si n lo kaakiri nipa idajo naa.
Awon ti ko te lorun n se iwode bee si ni awon ti ejo naa gbe n se idunnu kiri ilu.

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...