Home / Àṣà Oòduà / Iṣẹ́ ìránṣẹ́ kò sí fún ìmẹ́lẹ́ èèyàn – Tunde Bakare

Iṣẹ́ ìránṣẹ́ kò sí fún ìmẹ́lẹ́ èèyàn – Tunde Bakare

Fẹ́mi Akínṣọlá

Ayé ló bàjẹ́ tí ọmọ olè ń dájọ; oníkálukú mọ ẹ̀tọ́ tó yẹ́’.
Olùṣọ́ àgùtàn Tunde Bakare ṣàlàyé bí ìdámẹ́wàá ṣe bẹ̀rẹ̀ ninu Bíbélì àti pé kò si ẹni tí wọ́n gbé ìbọn tì pé dandan ni kó san ìdámẹ́wàá.
Ó ní iṣẹ́ ọwọ́ òun ni òun ń jẹ nítorí pé Ọlọ́run kìí pe ọ̀lẹ sí iṣẹ́ àlùfáà.
Bakare sọrọ nípa ijọba Muhammadu Buhari pé ó ti gbìyanju, nítorí pé èèyàn ni èèyàn ó máa jẹ́ .
Ó ní àkókò tó fún Buhari láti lọ , kí ẹlòmíì le tẹ̀síwájú láti ibi tí Buhari bá iṣẹ́ dé.
Bákan náà ló mẹ́nuba àjọṣepọ̀ òun àti igbákejì Ààrẹ Ọṣinbajo pé, Ẹ̀gbá méjì kò gbọdọ̀ ja ara wọn níyàn,ni ọ̀rọ̀ àwọn.

About ayangalu

x

Check Also

Èsì àyẹ̀wò tuntun Nàìjíríà fihàn pé “313” èèyàn ti gbàlejò Kofi 19 …àjọ NCDC

Èsì àyẹ̀wò tuntun Nàìjíríà fihàn pé “313” èèyàn ti gbàlejò Kofi 19 …àjọ NCDC À fi kí á bẹ Ọlọ́run kó bá wa dásí ọ̀rọ̀ àjàkálẹ̀ àrùn ajániláyà pàtì yìí, bí àwọn tó ní kòrónáfairọ̀ọ̀sì ní Nàìjíríà ti ń peléke sí i báyìí,lẹ́yìn tí àjọ NCDC tún kéde okòólélọ́ọ̀dúnrún dín méje èèyàn tí èsì àyẹ̀wò wọn sẹ̀sẹ̀ jáde. Ní báyìí, èèyàn ẹgbẹ̀rún méje, àti . òjìlélẹ́gbẹ̀rin dínkan (7839) ni àkọsílẹ̀ wà pé ó ti ní àrùn náà ní Nàìjíríà. Àkójọpọ̀ ...