Home / Àṣà Oòduà / Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo

Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo

Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo
Láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí
Eledua jowo maa so wa pelu ijamba ina to n sele lasiko eerun yii.
Lojiji ni ijamba tun be yo ni oja gbaju-gbaja Amu ti o wa ni ilu Mushin ni ipinle Eko.


Oja yii ni won ti n ta awon igi ikole,abesitoosi ikole ati awon ohun ikole miiran gbogbo.


Awon eso panpana tete de ibi isele yii sugbon epa ko boro ni oro ina naa. Gbogbo bi won se n da omi sii lo n da bii igba ti won da epo petiro si ina naa.
Dukia to le ni bilionu naira lo sofo sinu isele buruku naa, eni to kan lo mo.
Isele yii ba opo eniyan lokan je nitori pe ko si eni ton le mo oja yii tele to maa gbo pe ina joo guruguru ti ko ni kawo mori.
Ko tii si eda Olorun kan to le so ohun to fa ijamba ina naa nitori pe awon onise monamona ko muna wa ni gbogbo asiko naa.
Ki Eledua ba wa dawo aburu duro.

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...