Home / Àṣà Oòduà / Àwon agbésùmòmí Boko Haram pa àwon àgbè àti àwon ará ìlú ní Borno.

Àwon agbésùmòmí Boko Haram pa àwon àgbè àti àwon ará ìlú ní Borno.

Ókéré jù àwon ènìyàn méèdógún (15) ni a gbó pé àwon agbésùmòmí Boko Haram pa nígbà tí won kolu ara won. Ìròyìn tí Orísun àwon figilanté gbé ni wípé òpò àwon ará ìlú ní won sì ń wá léyìn Ìsèlè tí ó selè ní Jakete ní ìjoba ìbílè Konduga, agbègbè kan ní ìpínlè Borno. Ní kété agogo méwàá òwúrò àná ni won yín ìbon pa wón nínú oko won, tí a sì ń wá àwon obìnrin àgbè méfà.

Orísun àwon figilanté ti ìbílè náà jé kí ó di mímò wípé àwon àgbè náà gbìyànjú láti bó sùgbón agbára won kò ká àwon agbésùmòmí yìí…

Continue after the page break for English Version

About oodua

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

Aáyẹ tí ó de bá àṣà

Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àṣà máa ń yí padà nípa aṣo wíwọ̀, ìgbéyàwó, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ, lóde-òní, ètò ẹ̀kọ́ àti ìwà ọ̀làjú tó gbòde kan ti ṣe àkóbá fún àṣà ní àwọn ọ̀nà wọ̀nyí: (a) Ìwọsọ wa kò bójú mu mọ́. (b) Àṣà ìkíni wa kò ní ọ̀wọ̀ nínú mọ́. (d) Kí’yàwó ilé má mọ oúnjẹ ìbílẹ̀ ṣè mọ́. (e) A kò mọ ìtumọ̀ àrokò tí a ń kọ́ àwọn ọmọ wa mọ́. (ẹ) A kò fi èdè ...