Home / Àṣà Oòduà / Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ojó mánigbàgbé ní ilé-èkó gíga Obafemi Awolowo university (OAU).

Ìsèlè burúkú gbáà ní Óní selè ní ojó kewàá osù keje odún 1999 ní ilé-èkó gíga ifáfitì Obafemi Awolowo university nígbà tí èmi oní inú ire sì gba ibè lo.

Afrika se béè Ó ta èjè rè sílè fún àwon akékòó ilé-èkó yí láti dènà egbé òkùnkùn láti ìgbà náà ni àláfíà, ìfòkànbalè ti wà nínú ogbà yí. Njé ó wá ye kí á gbàgbé ojó yí bí?

Èní lópé odún mókàndínlógún tí Afrika kú fún wa, kí ló wá dé tí a kò le polongo “kí egbé òkùnkùn wá sí òpin ” kí lódé tí a kò le rántí èjè tí Óní kú fún akékòó?

Akoni ni Afrika ejé kí á se ayeye ìrántí fun, kí á kí àwon ebí rè wípé wón kú afárárekù eni rere..

Njé Ìwo tí setán láti gbógun ti egbé òkùnkùn bí?.

About Awo

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

A kì í wípé kí ọmọ olówó kó má se yín gan-an gan-anBó bá ṣe yín gan-an gan-an a o ni fètè ìwọ̀fà boA dífá fún Ọ̀rúnmìlà wọ́n ní kí baba kó fi ẹbọ araa rẹ̀ sílẹ̀Wọ́n ní Ẹbọ ayé gbogbo ni kí baba o seỌ̀rúnmìlà ní kí ọmọ Osó kó mà kú oBaba ní k’ọ́mọ Àjẹ́ kó yèNítorí wípé ẹbọ ayé gbogbo ni mo nseIre oo