Home / Àṣà Oòduà / Òòsà Roman lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó alárédè ti Oritsefemi àti ìyàwó rè, Nabila Fash, níbi tí ó ti wo aso tí àyà rè hàn.

Òòsà Roman lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó alárédè ti Oritsefemi àti ìyàwó rè, Nabila Fash, níbi tí ó ti wo aso tí àyà rè hàn.

   Gbajúgbajà tí olórun fún ní èbùn tí ó bùáyà, tí a mò sí òòsà obìnrin ti ilè Roman lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó alárédè ti Oritsefemi àti Nabila Fash pèlú àyà rìwòwò tí olórun fún lo sí ibi ayeye ìgbéyàwó ìbílè Oritsefemi ní Lekki ní ìlú Eko.

About Awo

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

Aáyẹ tí ó de bá àṣà

Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àṣà máa ń yí padà nípa aṣo wíwọ̀, ìgbéyàwó, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ, lóde-òní, ètò ẹ̀kọ́ àti ìwà ọ̀làjú tó gbòde kan ti ṣe àkóbá fún àṣà ní àwọn ọ̀nà wọ̀nyí: (a) Ìwọsọ wa kò bójú mu mọ́. (b) Àṣà ìkíni wa kò ní ọ̀wọ̀ nínú mọ́. (d) Kí’yàwó ilé má mọ oúnjẹ ìbílẹ̀ ṣè mọ́. (e) A kò mọ ìtumọ̀ àrokò tí a ń kọ́ àwọn ọmọ wa mọ́. (ẹ) A kò fi èdè ...