Awon arije ni madaru, ika, odaju, ole, wobia, wonbiliki le po ni Naijiria loooto, sugbon awon eniyan rere ko ti tan lawujo wa. Okan ninu won ni alase ile epo Bovas to kale silu Ibadan. Bakan naa ni awon eniyan ...
Read More »Ijamba oko niluu Eko lojo odun keresimesi
Ti e ba muti, e ma wako; ti e ba wako, e ma muti. Okunrin kan lo koja lo sorun lojo odun keresimesi to koja yii ni akoko ti gbogbo eniyan n yo ayo iwasaye Jesu olugbala araye. Ijamba oko ...
Read More »Owo ti te Jaguda, Mohammed Isah to lu komisanna olopaa meji ni jibiti
Sebi ojo gbogbo ni tole, ojo kan pere ni tolohun. Owo awon olopaa ilu Eko ti te omo gambari onijibiti kan ti oruko re n je Mohammed Isah, to lu komisanna ipinle Ondo ati Anambra ni jibiti. Omokunrin onijibiti naa ...
Read More »Ikini odun lati owo Olayemi Olatilewa Oniroyin Agbaye
Olayemi, odun to n bo yii, odun emi ati iwo ni. Eyin e fota sile ki won ma gbogun. E fika eniyan sile ki won ma soogun. Mo tile tun gbo wi pe awon kan tun lo n bogun onire. ...
Read More »IROYIN OWURO ose yii ti jade ooo
Iru iku wo lo pa Sikiru Ayinde Barry Wonder? Inu iwe Iroyin Owuro ose yii ni e o ti ri. E gbiyanju ke e bere lowo fendo yin. Ogorun naira pere ni.
Read More »Yinka Ayefele sodun fun awon alaini ati omowewe
Aimoye awon omo wewe ni won pejo si bi ayeye odun keresimesi ati babakeresi ti ile ise redio Fesh FM ti Yinka Ayefele eleyii to waye ni Music House, ile orin Ayefele, to kale siluu Ibadan. Asekagba naa lo waye ...
Read More »“Oju Mimiko ni PDP yoo fi poora nipinle Ondo” – Oloye egbe APC
Okan pataki ninu awon oloye egbe APC nipinle Ondo, Niran Sule-Akinsuyi, ti so yanya wi pe niseju Gomina Olusegun Mimiko ni egbe oselu PDP ipinle naa yoo fi di ohun a-fi-seyin teegun fiso. Oro yii lo n so nigba to ...
Read More »Faleke n mura ija nipinle Kogi *Omo oloogbe Abubakar Audu n be leyin re.
*Omo oloogbe Abubakar Audu n be leyin re. *Kilode ti Tinubu ko da soro naa? Lati Ọwọ Olayemi Olatilewa Lojo Aje to koja yii ni rugudu ti n lo lagbo oselu nipinle Kogi tun bureke si i nigba ti Ogbeni ...
Read More »“Kosi ona ti a fe gbegba, ijoba ni lati yo owo iranwo ori epo kuro” – Oyegun
Alaga egbe oselu APC, oloye John Odigie-Oyegun ti fi da awon omo Naijiria loju wi pe, kosi ipadaseyin ninu yiyo owo iranwo ori epo robi. Oyegun lo n soro yii nigba ti n gbalejo awon iko kan lati inu egbe ...
Read More »Aregbesola ya ₦130m lati ko ile iwe girama kan
Iroyin Lati Ọwọ Olayemi Olatilewa Gomina Rauf Aregbesola tipinle Osun ti lo si ileewe girama, Olufi Middle School to kale si Gbongan ni Ijoba Ibile Ayedaade to wa nipinle naa. Nibi ayeye ti won ti n si ileewe naa ni ...
Read More »