Home / Àṣà Oòduà / Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn covid-19

Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn covid-19

Raymond Dokpesi sé̩gun àrùn coronae̩i

Aja to rele Ekun to bo, o ye ki a kii ku ewu.
Gbajugbaju oludasile ileese redio ati telifison Ray power ati AIT ni o se alabapade ajakale arun coronavirus ni nnkan bii ose meji to koja lo.
Arun yii ko mu oun nikan, o tun mu mefa miiran ninu ebi re. Oni yii ni ori ko alagba naa yo pelu awon ebi re mefeefa.
Oluulu Naijiria, Abuja ni won ti ģba iwosan tiwon, ni ibi ti won ti n se itoju awon ti ajakale naa ba ko lu.


Gbogbo awon ebi, ore ati ojulumo lo ti bere si ni ki alagba naa ku oriire. Nitori pe aisan naa buru de bii wo pe ko mo olowo bee ni ko mo talaka sugbon Eledua ko won yo.

Ìròyìn láti o̩wó̩ Yínká Àlàbí

About ayangalu

x

Check Also

Sanwo olu

Ìpínlẹ̀ Eko ní ìfojúsùn ìpè pàjáwìrì ìsẹ́jú márùn-ún péré

Ìpínlẹ̀ Eko ní ìfojúsùn ìpè pàjáwìrì ìsẹ́jú márùn-ún péré Yínká Àlàbí Ile-iṣẹ Aṣẹ ati Iṣakoso Pajawiri ti Ipinle Eko sọ pe awọn ti setan lati dahun si awọn ipe pajawiri ni ipinlẹ Eko laarin isẹju marun-un pere.Olùdarí Àgbà fún ilé-iṣẹ́ náà, Ọ̀gbẹ́ni Femi Giwa, sọ èyí ní ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò kan pẹ̀lú awọn oniroyin ní ìlú Èkó.Giwa sọ pé àfojúsùn ilé-iṣẹ́ náà ni láti dín àkókò tó wà láàrín ìyè àti ikú kù nípa rírí dájú pé ìdáhùn náà wáyé láàrín ìṣẹ́jú ...