Awon onpitan wu itan Emir Kano ana jade. Won ni oro re dabi egun ti baba baba re ti se sile. Won ni odun 1963 ni ede aiyede waye laare Emir Mohammed Sanusi to je baba eni ti gomina yo ...
Read More »Àwọn obìnrin tọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn
Àwọn obìnrin tọ́kasí pàtàkì ìbáraẹnidọ́gba láárin ọmọnìyàn Ọjọ́ kẹjọ ọdọọdún ni àyájọ́ àwọn obìnrin lágbàáyé níbi tí gbogbo àgbáyé tí ń kọjú sí àwọn obìnrin láti yòǹbó àwọn iṣẹ́ takuntakun tí wọ́n gbé ṣe láì nọ́ọ́ní onírúurú ìpèníjà, ẹ̀dùn ọkàn ...
Read More »Ènìyàn mó̩kàndínlógójì ti ní àsepò̩ pèlú alárùn coronavirus l’Ogun
Iberu bojo ti po gan-an ni ipinle Ogun bayii, paapaa julo lati igba ti ayewo ti fihan pe alarun buruku kan ti wo orileede yii lati orileede Italy.
Read More »El- Rufai bá e̩bí ènìyàn 51 ké̩dùn
El- Rufai bá e̩bí ènìyàn 51 ké̩dùnNnkan buruku sele ni ilu Giwa ati Igali ni oru ojo aiku moju ojo Aje.Awon adihamora ni won tun ya bo awon ilu ati abule ni ipinle Kaduna ti won si bere si pa ...
Read More »Ilé-ẹjọ́ fi mílíọ̀nù mẹ́wàá náírà fa APC létí
Ejo ti ile-ejo giga to fi ikale si ilu Abuja da ni ojo ketala, osu yii ni egbe oselu APC ni awon ko fara mo.
Read More »Òògùn náà(Chloroquine phosphate) lè ṣiṣẹ́ fún ìtọ́jú àrùn a jà má mààlà (Coronavirus ) tó ń tàn káàkiri.
Òògùn náà(Chloroquine phosphate) lè ṣiṣẹ́ fún ìtọ́jú àrùn a jà má mààlà (Coronavirus ) tó ń tàn káàkiri. Fẹ́mi Akínṣọlá Ọ̀rọ̀ yìí dà bí ọ̀rọ̀ ìwé mímọ́ tó sọ pé ” òkúta táwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀ sílẹ̀, ló di pàtàkì igun ...
Read More »Nnkan méje ti yóò yipada àti meje ti kò ni yi pada lẹ́yìn ti ilẹ Gẹ̀ẹ́si ti kuro labẹ EU
Lẹ́yin ọdún mẹ́ta lílọ bibọ̀ lórí ọ̀rọ̀ Brexit, ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́ṣì padà kúrò lábẹ́ EU ní aago mọ́kànlá alẹ́ ọjọ́ Jimọ ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n Oṣù kínní ọdún 2020.
Read More »Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’Ekoo
Ò̩pò̩ dúkìá sègbé sínú ìjàm̀bá iná ló̩jà Amu l’EkooLáti o̩wó̩ Yínká ÀlàbíEledua jowo maa so wa pelu ijamba ina to n sele lasiko eerun yii.Lojiji ni ijamba tun be yo ni oja gbaju-gbaja Amu ti o wa ni ilu Mushin ...
Read More »Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue
Ilé-ẹjọ́ tó ga jù ní Samuel Ortom náà ló tún jáwé olúborí ní BenueLáti ọwọ Yínká Àlàbí Iroyin yajoyajo to wole bayii lo n jeri sii bi ile ejo to ga ju lo to fi ikale si ilu Abuja se ...
Read More »Ìjọba Àpapọ̀ Kò Gbẹ́sẹ̀lẹ̀ Lé Owó Tó Tọ́ Sáwọn Ìjọba Ìbílẹ̀ L‘ọyọ
Lórí ọ̀rọ̀ kan tó gbà gboro kan pé àgbẹjọrò àgbà orilẹ̀-èdè Naijiria, Abubakar Malami ti pàṣẹ fún gómìnà ìpínlẹ̀ Oyo láti gba àwọn alága káńṣù ti wọ́n yọ nípò pada, Ìjọba Ọyọ ti fèsì lórí ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Read More »