Home / Author Archives: Lolade

Author Archives: Lolade

Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn

Adelabu tún gbé Ṣeyi Makinde lọ sí ilé ẹjọ́ kòtẹ́milọ́rùn Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn àgbà ní bí o bá nídíì,arúgbó ò gbọdọ̀ sunkún ọmú.Bayo Adelabu ti ẹgbẹ́ òsèlú APC ní òun kò faramọ́ ìdájọ́ Àjọ Elétò Ìdìbò tó ní Ṣeyi Makinde ...

Read More »

Awada Toni: Omo Ibadan

Read More »

Ifá náà ki bayi wípé: Adaku Adaoku

Ekaaro eyin eniyan mi, aojiire bi, aku ise ana o, a si tun ku imura toni, gegebi a se mo wípé oni je ojó isegun, ogun buburu yio se ninu igbesi ayé wa loni o Àse. E jeki a fi ...

Read More »

Olúbàdàn kìlò kí won má se jàgídíjàgan bí odún egúngún se fé bèrè.

Gégé bí odún egúngún odoodún se ma bèrè l’óla, ojó ajé, ní ìlú Ibadan, ní ìpínlè Oyo, Olúbàdàn ti ilè Ibadan, oba Saliu Akanmu Adetunji ti pè fún àláfíà láti òdò àwon eléégún àti àwon tí ó ń tèle tí ...

Read More »

Àwòrán láti ìlú olómìnira kan tí a mò sí Ewédú àti ìgbálè

Àwòrán láti owó omo oòduà rere. Àwòrán láti ìlú olómìnira kan tí a mò sí Ewédú àti ìgbálè (a fé béè, èrín yakata). Ta ló tún n’ìfé àwòrán láti ìjìnlè ìlú yorùba? N’ísàlè ni àwòrán àjò lo sí ìlú Iseyin ...

Read More »

Olólùfé gbajúgbajà olórin Davido sòrò nípa irun abíyá rè tí kò fá. “Ra igi fífá-irun àádóta náírà (#50)nínú bílíònù lónà ogbòn re.

Àwon olólùfé gbajúgbajà olórin tí a mò sí Davido sòrò nípa irun abíyá rè tí kò fá. “Ra igi fífá-irun àádóta náírà (#50)nínú bílíònù lónà ogbòn re. Davido le jé eni tí àwon ènìyàn féràn sùgbón ìyan kò so pé ...

Read More »

Aawọ ni Oshodi: Oluomo, Talonskibo, Harmburger Ati Oluwo.

        English Version Continue after the page break

Read More »

Ekaaro eyin eniyan mi, aojiire bi?

Eku ise ana o, a si ku popo sinsin odun o emin wa yio se pupo loke erupe ninu alaafia ara o, bi a se njade lo loni eledumare ninu aanu re yio fi iso ati aabo re bowa lowo ...

Read More »

Aderupoko lori Eto Gbajumo Osere

Read More »

Bobo B lori Eto Gbajumo Osere

Read More »