Home / Àṣà Oòduà / Banky W àti Adesua Etomi fi enu ko ara won lénu níbi ayeye ìgbéyàwó alárédè won ní orílè èdè South Africa .

Banky W àti Adesua Etomi fi enu ko ara won lénu níbi ayeye ìgbéyàwó alárédè won ní orílè èdè South Africa .

” O le wá fi enu ko ìyàwó lénu báyìí” ni ó ma n dùn jù nínú ìgbéyàwó, tí kò bá rí béè Banky W àti Adesua kò bá má se tó báyìí, won ti fi enu ko ara lénu jù tí àwon àlejò fi so wípé ó ti pòjù, tí won fi pariwo wípé “ó ti tó”.
Èyí le múni ronú o .
Tokotayà tí ó rewà yí kí ara won.

About Awo

One comment

  1. Emi yin a guun oo.. Ase

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

Aáyẹ tí ó de bá àṣà

Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àṣà máa ń yí padà nípa aṣo wíwọ̀, ìgbéyàwó, àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ, lóde-òní, ètò ẹ̀kọ́ àti ìwà ọ̀làjú tó gbòde kan ti ṣe àkóbá fún àṣà ní àwọn ọ̀nà wọ̀nyí: (a) Ìwọsọ wa kò bójú mu mọ́. (b) Àṣà ìkíni wa kò ní ọ̀wọ̀ nínú mọ́. (d) Kí’yàwó ilé má mọ oúnjẹ ìbílẹ̀ ṣè mọ́. (e) A kò mọ ìtumọ̀ àrokò tí a ń kọ́ àwọn ọmọ wa mọ́. (ẹ) A kò fi èdè ...