Home / Àṣà Oòduà / Adanwo ni oro ile aye: Iku Abubakar Audu gba arojinle

Adanwo ni oro ile aye: Iku Abubakar Audu gba arojinle

Titi di akoko yii, enikeni ko le so pato ohun to sekupa oludije ipo gomina labe egbe oselu APC ni ipinle Kogi, Abubakar Audu. Se ise aye ni abi amuwa Olorun oba? Ohun ti ko ye enikan, kedere ni niwaju Olorun Oba. Olayemi Oniroyin, joojumo ni mo n kogbon aye. Gbogbo igba ni mo si n ran ara mi leti wi pe asan ni duniyan, omulemofo nigbogbo re pata je. Sugbon adura kan lo wu mi ti mo fe se fun gbogbo eyin ololufe Olayemi Oniroyin, ojo ti ire ayo yin ba wole de, imo esu ko ni ba ayo naa je. Odun n lo sopin, ibanuje, o kere, o tobi, ko ni wo ile wa. A ko ni rogun ekun, idaamu, wahala, ipayinkeke ko ni yale enikeni wa. Amin.

About oodua

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

ALÁÀFIN

Ó Pọ́dún Mẹ́ta Lónìí Tí Aláàfin Adéyẹmí Re Barà.

Kò sẹ́ni tí ó ju sáyé, gbogbo wa la ó dìtàn. Aláàfin Àtàndá ti kópa ti wọn, wọ́n ti lọ. Ọdún kẹta rèé tí Aláàfin Ọláyíwọlá ọmọ Adéyẹmí yíjú kúrò níhìn-ín, Ọláyíwọlá kọjú sáwọn aláṣekù, Baba bá wọn lọ. Iṣẹ́ tí wọ́n ṣe é lẹ̀ là ń sọ, tó dìròyìn. Bí a ti ń sọ ọ̀rọ̀ nípa Ọmọ Ìbírònkẹ́ lónìí, àsìkò ń bọ̀ tí àwọn kan náà ó sọ nípa tiwa. Kí layé á sọ nípa tèmi-tìrẹ? Ìlẹ̀pa dòdò kó ...