“Kosi ona ti a fe gbegba, ijoba ni lati yo owo iranwo ori epo kuro” – Oyegun
Alaga egbe oselu APC, oloye John Odigie-Oyegun ti fi da awon omo Naijiria loju wi pe, kosi ipadaseyin ninu yiyo owo iranwo ori epo robi. Oyegun lo n soro yii nigba ti n gbalejo awon iko kan lati inu egbe ...
Read More »
Àṣà Oòduà Àṣà Oòduà
