Home / Àṣà Oòduà / Ènìyàn O̩gbò̩n Ti Lùgbàdì Coronavirus Ni Naijiria

Ènìyàn O̩gbò̩n Ti Lùgbàdì Coronavirus Ni Naijiria

Ènìyàn o̩gbò̩n ti lùgbàdì coronavirus ni Naijiria
Ìròyìn láti o̩wo̩ Yínká Àlàbí

Afi ki Eledua maa ko wa yo ni orileede yii. Bi ere bi awada, ajakale arun kogboogun (covid-19) ti mu eniyan ogbon di asiko ti a n ko iroyin yii jo ni ojo aiku, ojo kejilelogun, osu keta odun 2020.

Gege bi ajo to n mojuto eto ilera naa, N C D C, (Nigeria centre for disease control) se gbee sita.
Won ni mejilelogun lo yoju ni ipinle Eko, merin ni Abuja, meji ni Ogun, okan ni Oyo nigba ti okan to ku naa wa lati Ipinle Ekiti.

Gbogbo ileewe lo ti fere wa ni titi pa, opo osise lo ti wa nile sibe won ni ki a je ki imototo wa po sii lasiko yii.

About ayangalu

x

Check Also

ojo keji

Ó San Owó Ilé Ìwé Mi Títí Mo Fi Jáde, Ṣùgbọ́n Mo Fi Májèlé San!

Àti ilé ìwé e gírámà ni èmi àti Kọ́lá ti jọ ń fẹ́ ra wa. Àwọn òbí i mi ò kí ń fẹ́ rí Kọ́lá pẹ̀lú u mi nítorí ààfín ni. Nígbà tí mo fẹ́ wo ile ìwé gíga ni bàbá à mi ní àìsàn an rọ́pá, rọsẹ̀,ọpẹ́lọpẹ́ kọ́lá tó san owó ilé ìwé è mi láti ìgbà tí mo wolé ẹ̀kọ́ gíga títí mo fi jádé. Nígbà ti mo lọ ṣe agùnbánirọ̀ mo pàdé sẹ́nátọ kán,èmi àti ẹ̀ sì ...