Home / Àṣà Oòduà / Ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún, Ogogo.. ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ eré bọ́lùú wáyé

Ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún, Ogogo.. ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ eré bọ́lùú wáyé

Ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún, Ogogo.. ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ eré bọ́lùú wáyé

Fẹ́mi Akínṣọlá

Ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà Yoruba to tí ta gbòǹgbò káàkiri àgbáyé ni Alhaji Taiwo Hassan tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí Ogogo ọmọ kúlódò jẹ́. Nítorí náà kò ya ni lẹ́nu nígbà tí ètò lónírúurú gbode kan fún ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún tó ṣe. Lára àwọn ètò náà ni ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ láàrin ikọ̀ ogogo, (Ogogo All stars) àti ikọ̀ to jẹ́ ti olórí Ilé aṣòfin ìpínlẹ̀ Eko, ( Obasa All stars).
àá áà àà éé èè ẹ́ ẹ́ẹ̀ù ùẹ̀ ùẹ̀ ẹ̀ẹ̀ íí ìì óó òò ọ́ọ́ ọ̀ọ̀ ọọ úú ùù àà
Nígbà tí ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà yóó fi parí ní pápá ìṣeré Agége, góòlù méjì làwọn ikọ̀ Obasa All Stars fi gbẹyẹ mọ́ ikọ̀ Ogogo lọ́wọ́ o.

About ayangalu

x

Check Also

ojo keji

Ó San Owó Ilé Ìwé Mi Títí Mo Fi Jáde, Ṣùgbọ́n Mo Fi Májèlé San!

Àti ilé ìwé e gírámà ni èmi àti Kọ́lá ti jọ ń fẹ́ ra wa. Àwọn òbí i mi ò kí ń fẹ́ rí Kọ́lá pẹ̀lú u mi nítorí ààfín ni. Nígbà tí mo fẹ́ wo ile ìwé gíga ni bàbá à mi ní àìsàn an rọ́pá, rọsẹ̀,ọpẹ́lọpẹ́ kọ́lá tó san owó ilé ìwé è mi láti ìgbà tí mo wolé ẹ̀kọ́ gíga títí mo fi jádé. Nígbà ti mo lọ ṣe agùnbánirọ̀ mo pàdé sẹ́nátọ kán,èmi àti ẹ̀ sì ...