Home / Àṣà Oòduà / Orí kó ènìyàn márùn-ún yọ lọ́wọ́ coronavirus l’Ekoo

Orí kó ènìyàn márùn-ún yọ lọ́wọ́ coronavirus l’Ekoo

Orí kó ènìyàn márùn-ún yọ lọ́wọ́ coronavirus l’Ekoo
Ìròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí

Alaisan marun-un ninu awon ti arun buruku covid-19 ti n ba finra lati bii ose meloo kan seyin gba idande. Yoruba bo “won ni alaare ko ki n ra si inu yara, bi o segun aisan, yoo fi ese ara re rin jade, bi o ba si yiwo naa, won a gbe oku re jade”.

Eyi lo sele si awon marun-un ti arun coronavirus ti n ba poo, ti won si segun arun naa, nitori pe gbogbo ayewo ti won se fun won lera-lera si gbee pe aisan naa ko si lara won mo.

Minisita eto ilera Dokita Osagie Ehanire ati ajo NCDC se tun n parowo si gbogbo omo Naijiria, won ni arun naa ko tii ni oogun kan gbogi nipa idi eyi, ki awon eniyan so ewe agbeje mowo. Ki onikaluku si gbe inu ile re gege bi gbogbo eka ijoba se n forere.

http://iroyinowuro.com.ng/2020/03/30/ori-ko-eniyan-marun-un-yo-lowo-coronavirus-lekoo/

About ayangalu

x

Check Also

seun kuti

Orí kó Seun Kuti yọ kúrò lọ́wọ́ ikú ní yàrá ìgbàlejò US

Mary Fágbohùn Olórin Afrobeat Seun Kuti ti fi ìrírí ibanuje ọkàn rẹ̀ ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà han nígbà tí ọta ibọn kan gúnlẹ̀ lójú fèrèsé yàrá igbalejo rẹ̀. O salaye ibapade to ba ni lẹru naa lori oju-iwe Instagram rẹ, o fi fidio ferese ti ọta ibọn naa bajẹ ati iho re han. Seun, ẹni ti o ṣalaye iyalẹnu, beere iwoye ti aabo ni Amẹrika. Ninu fonran naa, Seun Kuti sọ pe oun wa ninu yara igbalejo, ti oun n sinmi, ...