Home / Àṣà Oòduà / Seyi Makinde di gómìnà kẹ́ta tó kó àrùn Covid-19

Seyi Makinde di gómìnà kẹ́ta tó kó àrùn Covid-19

Oni ogbon ojo, osu keta ni ayewo gomina ipinle Oyo, Alagba Seyi Makinde jade, ti ayewo naa si gbee pe o ni arun naa. Oun ni o maa je eleeketa gomina ni orileede yii ti ayewo fihan pe won ni arun kokoro naa.


Gomina ipinle Bauchi, Bala Mohammmed ni o koko ni, ki ayewo to gbe ti gomina ipinle Kaduna , Nazir El-Rufai jade. Eyi lo mu ki gbogbo eka ijoba maa pariwo ki onile ko gbele nitori ajakale arun naa.

Arun naa ko mo olowo, bee ni ko mo talaka. Arun naa ko ni aponle fon egbe oselu to n se ijoba lowo de bi to maa ni fun egbe oselu ti ko se ijoba rara. Bi ojo ni arun naa se n rin, “eni ti eji re ri ni eji n pa”.

Seyi Makinde di gómìnà kẹ́ta tó kó àrùn Covid-19
Ìròyìn láti ọwọ́ Yínká Àlàbí

About ayangalu

x

Check Also

ojo keji

Ó San Owó Ilé Ìwé Mi Títí Mo Fi Jáde, Ṣùgbọ́n Mo Fi Májèlé San!

Àti ilé ìwé e gírámà ni èmi àti Kọ́lá ti jọ ń fẹ́ ra wa. Àwọn òbí i mi ò kí ń fẹ́ rí Kọ́lá pẹ̀lú u mi nítorí ààfín ni. Nígbà tí mo fẹ́ wo ile ìwé gíga ni bàbá à mi ní àìsàn an rọ́pá, rọsẹ̀,ọpẹ́lọpẹ́ kọ́lá tó san owó ilé ìwé è mi láti ìgbà tí mo wolé ẹ̀kọ́ gíga títí mo fi jádé. Nígbà ti mo lọ ṣe agùnbánirọ̀ mo pàdé sẹ́nátọ kán,èmi àti ẹ̀ sì ...