Home / Àṣà Oòduà / Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue

Ilé-ẹjọ́ Tó Ga Jù Ní Samuel Ortom Náà Ló Tún Jáwé Olúborí Ní Benue

Ilé-ẹjọ́ tó ga jù ní Samuel Ortom náà ló tún jáwé olúborí ní Benue
Láti ọwọ Yínká Àlàbí


Iroyin yajoyajo to wole bayii lo n jeri sii bi ile ejo to ga ju lo to fi ikale si ilu Abuja se da ejo oludije fun ipo gomina ni ipinle Benue, iyen Emmanuel Jime ti egbe oselu APC nu bi omi isanwo.


Awon adajo meje ti Adajo Olabode Rhodes-vivour je olori fun ni won se idajo naa ni nnkan bii ogbon iseju seyin.
Ile ejo ni gbogbo awijare egbe oselu APC ko lese nile, nipa idi eyi ki gomina Ortom ti egbe oselu PDP si maa se ijoba re lo ni alaafia.


Ti a ko ba gbagbe, ana ode yii naa ni ile ejo yii da ejo awon gomina merin nigba ti ti ipinle Imo waye ni ose to koja bi o tile je pe iwode si n lo kaakiri nipa idajo naa.
Awon ti ko te lorun n se iwode bee si ni awon ti ejo naa gbe n se idunnu kiri ilu.

http://iroyinowuro.com.ng/2020/01/21/ile-ejo-to-ga-ju-ni-samuel-ortom-naa-lo-tun-jawe-olubori-ni-benue/

About ayangalu

x

Check Also

ojo keji

Ó San Owó Ilé Ìwé Mi Títí Mo Fi Jáde, Ṣùgbọ́n Mo Fi Májèlé San!

Àti ilé ìwé e gírámà ni èmi àti Kọ́lá ti jọ ń fẹ́ ra wa. Àwọn òbí i mi ò kí ń fẹ́ rí Kọ́lá pẹ̀lú u mi nítorí ààfín ni. Nígbà tí mo fẹ́ wo ile ìwé gíga ni bàbá à mi ní àìsàn an rọ́pá, rọsẹ̀,ọpẹ́lọpẹ́ kọ́lá tó san owó ilé ìwé è mi láti ìgbà tí mo wolé ẹ̀kọ́ gíga títí mo fi jádé. Nígbà ti mo lọ ṣe agùnbánirọ̀ mo pàdé sẹ́nátọ kán,èmi àti ẹ̀ sì ...