Home / Àṣà Oòduà / Àwòrán : afurasí omo egbé òkùnkùn kan tí a mò sí Baddo ni owó tè ní Ikorodu.

Àwòrán : afurasí omo egbé òkùnkùn kan tí a mò sí Baddo ni owó tè ní Ikorodu.

Afurasí omo ògbó-n-tarìgì egbé òkùnkùn, Baddo, ni owó tè ní Ikorodu ní ìpínlè Èkó Lánàá tí osù kefà di ogbòn (June 30th) gégé bí àwon olùgbé àdúgbò se so, a rí Arákùnrin yí tí ó ń rìn káàkiri agbègbè Obafemi Awolowo, kí á tó dé ilé-ìwé Government Technical College Ikorodu, pèlú àdá àti àpò tí ó kún fún ègbin.

Nígbà tí won lo ba tí won sì bèèrè àwon ìbéèrè kan lówó rè, èsì rè kò dáńgájíá, kò le sàlàyé ara rè, ó so wípé àgbè ni òun àti wípé àwon ebí òun ti kú. Àwon àgbà àdúgbò náà kò jé kí àwon òdó dá sèríyà fun láti owó won, wón ri wípé wón fà á lé aeon olóòpá ní ilé-isé olóòpá Igbogbo lówó, níbi tí won ti ń fi òrò wa lénu wò……

Cntinue after the page break fro English Translation

About ayangalu

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

Òfún kò rẹ́tẹ̀ be yín

A kì í wípé kí ọmọ olówó kó má se yín gan-an gan-anBó bá ṣe yín gan-an gan-an a o ni fètè ìwọ̀fà boA dífá fún Ọ̀rúnmìlà wọ́n ní kí baba kó fi ẹbọ araa rẹ̀ sílẹ̀Wọ́n ní Ẹbọ ayé gbogbo ni kí baba o seỌ̀rúnmìlà ní kí ọmọ Osó kó mà kú oBaba ní k’ọ́mọ Àjẹ́ kó yèNítorí wípé ẹbọ ayé gbogbo ni mo nseIre oo