Home / Àṣà Oòduà / Eji Ogbe Verse

Eji Ogbe Verse

Jọ̀gbọ̀dọ̀ lẹ̀fọ́ lorúko ti Ifá ńjẹ́
Ẹ̀rọ̀ wọ̀ loyèe tẹ̀tẹ̀

Ayé kọpá
Ẹ̀sọ̀ lo gbà

Èle tán láye
Ẹ̀rò ló kù

A dífá fún Ìrókò Ẹlujù
Tí wọ́n ní ó máa so okùn
Kó tún máa so oyindẹ

Ìrókò kó o má so èle
Ẹ̀rọ̀ were nÌrókò ń so
Ẹ̀rọ.

Courtesy: Moyo Okedeji

About oodua

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

*

x

Check Also

“Ta Ní Ó Wà Kí Ayé Tó Wà? Ìtàn Àkọ́kọ́ Ìṣẹ̀dá Gẹ́gẹ́ Bí Ifá Ṣe Sọ Ó.”

Kò sí ohun ẹlẹ́mìí kankan láyé awo ilé Ayé ni ọ̀run àkọ́kọ́, ohun tí ó so kàrà tí kò sọ̀kalẹ̀, awo òde Ọ̀run ni ó ń pè é, gbogbo rẹ̀ jẹ́ òfìfo lásán, òfo pónbele, láìní ìpìlẹ̀, láìní ẹ̀dá kankan, Awo àárín gbùn-gbùn òde ni ó wí i, A dífá fún Ayé àti fún Ọ̀run, nínú ìkarawun ìgbín méjì tí ó ṣófo, kò sí ẹyẹ, kò sí ẹ̀mí tí ń gbé inú wọn, ìpìlẹ̀ kò tí ì sí, afẹ́fẹ́ kò ...