Home / Àṣà Oòduà (page 21)

Àṣà Oòduà

Àṣà Oòduà, Asa Ibile Oòduà. Oòduà (Yoruba) je okan ninu awon eya ti o laju ju lode aye yi. Lati igba ti alaye ti daye ni won ti ni eto ati ilana to kun nipa ohun gbogbo ti won nse ni igbesi ayee won.

Kini a npe eleyi ni ede kaaro o ojire?

Read More »

Ìdí tí Oluwo fi kọ Olorì rẹ̀ sílẹ̀ rèé

Ìdí tí Oluwo fi kọ Olorì rẹ̀ sílẹ̀ rèé Fẹ́mi Akínṣọlá Kábíèsí Oluwo ti ìlú Ìwó, Ọba Abdulrosheed Adewale ti kọ Olorì rẹ̀ Chanel Chin sílẹ̀. Agbẹnusọ fún Kábíèsí ọ̀hún, Alli Ibrahim fi ìdí ọ̀rọ̀ náà mulẹ fún akọ̀ròyìn. Bí ...

Read More »

Àhes̩o̩ ò̩rò̩ ni ikú Babangida

Aheso oro ni iku BabangidaYinka AlabiAriwo iku ajagunfehinti to o tun je Aare Ologun ni orileede yii tele ri, Ibrahim Babangida ni o gbode Kan.Ariwo yii po lori ero ayelujara lati idaji oni sugbon Ogbeni Kazim Afegbua ni iro ni. ...

Read More »

Èèmọ̀ rè é o !, Ìyàwó àfẹ́sọ́nà kú sínú Kànga, nígbeyàwó kọ̀la

http://iroyinowuro.com.ng/2019/12/14/eemo-re-e-o-iyawo-afesona-ku-sinu-kanga-nigbeyawo-kola/ Èèmọ̀ rè é o !, Ìyàwó àfẹ́sọ́nà kú sínú Kànga, nígbeyàwó kọ̀la Fẹ́mi Akínṣọlá À fi ká kún f’áàdúà kí ọjọ́ ayọ̀ ẹni ó má padà dọjọ́ ìbànújẹ́.Kí èṣù ó sì má ráàyè gbọjọ́ ẹ̀yẹ ẹni . À bí ...

Read More »

Ìlé ẹjọ́ rọ Obalufẹ̀ ti Ilé Ifẹ̀ lóyè

http://iroyinowuro.com.ng/2019/12/15/ile-ejo-ro-obalufe-ti-ile-ife-loye/ Ìlé ẹjọ́ rọ Obalufẹ̀ ti Ilé Ifẹ̀ lóyè Fẹ́mi Akínṣọlá Ó dà bí ẹni pé awuyewuye ìfinijoyè , ìyọnilóyè sì ń tẹ̀ẹ́wájú o , bí Ilé ẹjọ́ gíga ti ìpínlẹ Ọṣun ti pa á láṣẹ fún Ọbalúfẹ̀. ti ìlú ...

Read More »

Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn…Taiwo Hassan

http://iroyinowuro.com.ng/2019/12/12/opo-eeyan-lo-sa-fun-mi-nigba-ti-mo-dubule-aisan-taiwo-hassan/ Ọ̀pọ̀ èèyàn ló sá fún mi nígbà tí mo dùbúlẹ̀ àìsàn…Taiwo Hassan, Ògògó Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn àgbà ní bí ẹyìn ọ̀rọ̀ ò bá ì pọ́n, ẹnìkan kìí sí i ,bẹ́ẹ̀ gẹ́lẹ́ lọ̀rọ̀ rí bí gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò,n nì, ...

Read More »

Ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún, Ogogo.. ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ eré bọ́lùú wáyé

Ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún, Ogogo.. ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ eré bọ́lùú wáyé Fẹ́mi Akínṣọlá Ìlúmọ̀ọ́ká òṣèré tíátà Yoruba to tí ta gbòǹgbò káàkiri àgbáyé ni Alhaji Taiwo Hassan tí ọ̀pọ̀ èèyàn mọ̀ sí Ogogo ọmọ kúlódò jẹ́. Nítorí náà kò ya ni lẹ́nu ...

Read More »

Meet my Iyanifa!

Aboruboye meet my Iyanifa!

Read More »

Iléeṣẹ́ DSS tú Sowore sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ gbọọrọ ní àhámọ́

Iléeṣẹ́ DSS tú Sowore sílẹ̀ lẹ́yìn ọjọ́ gbọọrọ ní àhámọ́ Fẹ́mi Akínṣọlá Àwọn òṣìṣẹ́ DSS gbé Soworẹ lásìkò tí ó fi ń léwájú ìwọ́de “Revolution now”.Ìtúsílẹ̀ rẹ̀ ń wáyé lẹ́yìn tí ó ti lo ọjọ́ márùndíláàdóje ní hàhámọ́ àwọn DSS. ...

Read More »

Obi ni n bi arun

AboruAboyeAbosise..Ifa niiiiii Obi ni n bikuObi ni n bi arunObi ni n bi ofoObi ni n bi gbogbo ibi.Olodumare abawa fi obi biku, bi arun, bi ofo, bi gbogbo ajogun ibi aye wa o.Ase edumare. Sponsored by Asa Oodua Cola ...

Read More »