Home / Àṣà Oòduà (page 40)

Àṣà Oòduà

Àṣà Oòduà, Asa Ibile Oòduà. Oòduà (Yoruba) je okan ninu awon eya ti o laju ju lode aye yi. Lati igba ti alaye ti daye ni won ti ni eto ati ilana to kun nipa ohun gbogbo ti won nse ni igbesi ayee won.

Ènìyàn tí ó n gbé inú èkú láti ojó yìí tí a kò mò tí ó n jé lágbájá, àwòrán è rèé.

Okùnrin kan tí ó n gbé inú èkú fohún bí egúngún tí a mò sí lágbájá ni àwòrán hàn ní ìsàlé yí fún ànfààní àwa tí a kò da mò. Gbajúgbajà olórin a kó ni l’ógbón ni Lágbájá àwòrán rè ...

Read More »

Favour Iwueze ti Destined kids ti setán láti se ìyàwó.

Omo kékeré àná náà ti dàgbà, àdúrà wa ni wípé kí olórun má pa omo fún olómo. Favour Iwueze ìkan lára àwon omo kékeré ìgbàyan ti setán láti se ìgbéyàwó, kí ire ayò náà kárí.

Read More »

Oòni ti ìlú ilé-ifè darapò mó àwon mùsùlúmí ilé-ifè láti kírun ní ojó odún iléyà tí a mò sí Eid-el kabir.

Gégé bí a se mò wípé àwon omo léyìn músùlùmí sèsè se àsekágbá odún won ní léyìn tí won ti gba ààwè séyìn léyìn bí osù mejì àti òsè mélòó sèyìn. Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi ti darapò mó àwon músúlúmi ...

Read More »

Arákùnrin kan ni ó na ìyàwó rè, tí ó sì ba àwò ara ré je.

Arákùnrin kan ni a gbó wípé ó na ìyàwó rè tí ó sì dá àpá si lára, ládúrú bí won ti se n kó wa ní èkó lórí bí a se le gbé lókoláya tó. Bí ó tilè jé wípé ...

Read More »

Odún ìsèsi àgbáyé

Ogúnjó osù kejo (20/8) odoodún ni odún ìsèsi màa ń wáyé káàkiri àgbáyé. Ìlú kòòkan ni ó sì máa ń se odún náà sùgbón àwon ìpínlè Kan wà tí won máa ń se é papò bí ìpínlè Osun. Àjòdún odún ...

Read More »

Orin isese

Ao bo isese o, ao bo isese olowo o, isese o lao bo o, kawa to borisa o, BABA mi isese, IYA mi isese, lao bo o, kawa to borisa o, ORI mi isese, IKIN mi isese, lao bo o, ...

Read More »

Èèmò! Nígbà tí Gómìnà ìjòba ìpínlè Oyo wó ilé ìròyìn Yinka Ayefele ní ìlú Ibadan. Èyí kìí se àheso rárá, béè ní Gómìnà ìpínlè Oyo kò bá Gbajúgbajà olórin tí a mò sí Yinka Ayefele se eré rárá.

Ní òwúrò ànà tí se ojó Àìkú ní ariwo ta ní ìlú Ibadan ní ìpínlè Oyo nígbà tí ijoba ìpínlè náà pàse kí won wó ilé-isé ìròyìn ti Yinka Ayefele tí a mò sí Fresh Fm tí ó wà ní ...

Read More »

Gómìnà ìpínlè Osun kéde ojó Ajé(Monday) fún oludé fún ìsèsi tí yóò wáyé ní 20/08/2018.

Gómìnà ìpínlè Osun tí a mò sí Aregbesola ti kéde oludé fún gbogbo òsìsé ìjoba fún odún ìsèsí tí yóò wáyé ní òla ogúnjó osù kejo odún 2018.Asèyí se àmódún, ìsèsi á gbè wá oooo. Ìsèsi á gbè wá o.

Read More »

Àgbàrá òjò ní ìlú Benin látàrí òjò nlá tí ó rò lánàá.

Àgbàrá òjò ní ìlú Benin látàrí òjò nlá tí ó rò lánàá. Ní òpópónà Uselu ní ìlú Benin ti ìpínlè Edo ni àgbàrá ti gbalè gbalé léyìn òjò ñlá tí ó rò . òpòlopò okò ti omi gbé lo, òpó ...

Read More »

Èèmò lukutu pébé ní ilé-èkó gíga ìfáfitì ti Ilé-ifè : Nígbà tí akékòó kan ya wèrè nígbà tí ó n kàwé lówó.

Gégé bí a ti mo wípé òkan gbógì ní ilé-èkó gíga Òbafemi Awolowo University (OAU) jé ní orílè èdè Nìjíríà yí. Sà déédéé ni a gbó wípé arábìnrin kan tí ó jé akékòó ilé-èkó yí ya wèrè látàrí ìwé kíkà ...

Read More »