Àràbà Aworeni Adisa Makoranwale sun re.
òní tí ó jé ojó kokànlá osù kejo odún 2018 (11/8/2018) ni ètò ìgbé òkú baba wa tí ó sísè ní ojo ìségun tí ó jé ojó kokànlél’ógbòn osú keje odún tí a wà (31/7/2018) sí isà . Ìjo International ...
Read More »
òní tí ó jé ojó kokànlá osù kejo odún 2018 (11/8/2018) ni ètò ìgbé òkú baba wa tí ó sísè ní ojo ìségun tí ó jé ojó kokànlél’ógbòn osú keje odún tí a wà (31/7/2018) sí isà . Ìjo International ...
Read More »Gbajúgbajà olórin ti orílè èdè Nìjíríà, Timi Dakolo ti pín àwòrán ìyàwó rè àti àwon omo rè méta ní ìlú London, ó ko síbè wípé “wón tun ti dé baba wón tún ti dé”. Timi Dakolo ti ó jé omo ...
Read More »Olorì Badirat Olaitan, ìyàwó Aláàfin Òyó, Oba Lamidi Adeyemi kékeré, ti parí ifáfitì ní ilé-èkó gíga ifáfitì ti ìlú Ibadan tí a mò sí University of Ibadan. Bí omo bá dára ká so, ó ye kí á yé olorì sí ...
Read More »Ilé Ẹjọ́ Gíga Orílẹ̀-Èdè Braṣil: Ẹ Dáàbò bo Ẹ̀sìn Ìbílẹ̀ Aláwọ̀ Dúdú (Yoruba version by Akin Ogundiran) Àbádòfin kan ti kalẹ̀ ní ìlú Rio Grande do Sul ní ilẹ̀ Braṣil tí yô ká àwọn ẹlẹ́sìn ìbílẹ̀ aláwọ̀dúdú lọ́wọ́kò láti máa ...
Read More »A kú àmójúbà *Oṣù Ògún (August) tuntun.* Oṣù ìdùnnú ni yóò jẹ́ láṣẹ Èdùmàrè. Gbogbo àdáwọ́lé wa ló máa yọrí sí rere. Aboyún ilé á bí wẹ́rẹ́, àgàn á tọwọ́ àlà bọ osùn. Gbogbo ẹni tó ń ṣòwò yó jèrè, ...
Read More »Oba Aworeni Makonranwale Adisa ti re ìwàlè àsà, baba ti lo bá àwon baba ńlá rè. Olúsèse, Àràbà àgbáyé ti dágbére wípé Ó dígbà fún aráyé, baba ti lo rè é bá àwon baba ńlá rè ní ìwàlè àsà. Ó ...
Read More »Ni Àná tí ó jé ogbòn-ojó osù keje odún 2018, ni eka-èkó ìmò àti Àsà ti ilé-èkó gíga ifáfitì ti Obafemi Awolowo university se odún oúnje àti ìdánimò. Òjògbón Wole Soyinka kò gbéyìn rárá Baba náà péjú pésè níbi odún ...
Read More »Gégé bí a ti mò wípé ilé-ifè jé ìlú tí ilé-èkó gíga wà, tí ó sì kún fún àwon akékòó bíi àwon akékòó ilé-èkó gíga ifáfitì ti Obafemi Awolowo university (OAU) àti ilé-èkó gíga ifáfitì ti Oduduwa university ilé-ifè ...
Read More »Simi tí síde ayeye tí Jannie, Jazz àti Whisky pè ní ìlú Abuja ní alé ojó náà, Simisola jungle ní orí ìtàgé láti kí eni ńlá, èníyàn pàtàkí àti gbajúgbajà olórin láti dá àwon èníyàn lárayá papò. Ògbóntarìgì olórin tí ...
Read More »Ní òwúró ojó àíkú tí se èní,ojó kokàndínlógbòn osù keje odún 2018 ni òjò yí bèrè tí ó sì kò tí kò dáké di bíi agogo márùn-ún ìròlé. Èyí fa kí àgbàrá ya wo ilé tí ó pò ní òpópónà ...
Read More »