Asojú ilé-ìgbìmò asòfin Ademola Adeleke, ni a rí tí ó n jó pèlú àwon arewà.
Àwòrán ègbón Davido, asojú ilé-ìgbìmò asòfin ní bi tí ó ti n jó láàrin àwon arewà…
Read More »
Àwòrán ègbón Davido, asojú ilé-ìgbìmò asòfin ní bi tí ó ti n jó láàrin àwon arewà…
Read More »Arákùnrin ará Cameroon ni ó fi igi oparun gbé kúlà yí, eléyìí tún ya ni lénu ooo…ogbón kìí pé ní ilé ayé sha…
Read More »Ní àárò ojóbò, ojó kerìndílógún osù kèwá, (26/10/2017) ilé-ìwé Obafemi Awolowo University (OAU) àti agbègbè rè pàdánù omo ilé-ìwé kan tí ó n jé Afolarinmi Mercy tí ó wà ní ìpele àkókó (100level) ní eka èkó Micro biology…
Read More »Ìyá omo Runtown, Selena leath pín sí orí èro ayélujára àwòrán sáájú àti léyìn òun àti Runtown pèlú omokùnrin won, Zamar…
Read More »À béè rí nkan, e ri bí won se se jómúrégí papò! Won bá ara won mu gan ni…
Read More »Àwòrán ìgbà èwe ni ní tòótó fún gbajúgbajà òsèré Odunlade Adekola. Táà bá ní pa iró owó dáa l’ára…
Read More »Òdómobìnrin orílè-èdè Nàíjíríà ni ó pinnu láti se ayeye ojó ìbí ní àrà òtò, nígbà tí a ri tí ó n pín oúnje àti àwon nkan míràn fún àwon aláìní, omodé àti àwon èèyàn míràn . ònà ni ...
Read More »Oba orin Sunny Ade àti Flavour dìjo dá àwon ènìyàn l’ára yá lórí ìtàgé. Pèlú èrín ojú Flavour n se ni ó dà bí eni wípé inú rè dùn láti pàdé oba orin…
Read More »Gégé bí Innocent se so, olùsò àgùntàn rè pastor David Ibiyeomie ni won fún ní okò bògìnì tí ó wà ní ìsàlè yí gégé bi èbùn ojó ìbí rè, sé kò dùn gbó l’étí ni?. Ó ye kí ...
Read More »Òpolopò ènìyàn ni kò mo ìyàtò láàrin *IFÁ àti OLÓDÙMARÈ*. Òrò ni ifá, èyí tí ó ti enu Olúdùmarè wá tí ó fi rán *ÒRÚNMÌLÀ*
Read More »