Home / Àṣà Oòduà / Ṣàgbẹ̀lójú yòyò, ni ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré…. òjòpagogo

Ṣàgbẹ̀lójú yòyò, ni ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré…. òjòpagogo

Ṣàgbẹ̀lójú yòyò, ni ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré…. òjòpagogo

Fẹ́mi Akínṣọlá

Awọn agba bọ,wọn ni purọ n niyi,ẹwu ẹtẹ nii da bolowo ẹ lọrun lo mu
gbajugbaja agba ọjẹ oṣere Yoruba, Razak Ọlayiwọla ti gbogbo eeyan mọ si Ojopagogo bi o se sọrọ lori ohun to n ṣẹlẹ laarin awọn oṣere Yoruba.
O pabi ,o yabidun ọrọ lori awọn oṣere Yoruba ti wọn n gbe ara wọn sori ayelujara ati awọn to n gberaawọn gẹṣin aayan peraawọn ni n ti wọn ko jẹ .
Ojopagogo ni ere ṣiṣe a maa parọ mọ eeyan ni oju aye.
O ni awọn ipa olowo ti awọn n ko ninu ere ko sọ pe olowo ni awọn oṣere tiata loju aye.
AbdulaRazak ni ko si ohun to buru lati gbe oore Ọlọ́run sojutaye ṣugbọn, iwọntunwọnsi ni gbogbo nnkan.
O pakiyesi awọn eeyan si igbe aye awọn agba oṣere bii Ogunde, Baba Salah atawọn eekan mii,pe wọn kii fẹkọ tana fawọn eeyan.
Agba oṣere yii ko sai gba awọn oṣere to ku nimọran lati ṣe jẹjẹ nitori piparọ lori ayelujara kii jẹ ki eeyan ri alaanu.
O ni ki awọn ọdọ iwoyi ṣe pẹlẹ pẹlẹ, ki wọn ma ba a sare mọto kọlu kẹkẹ boruko ẹbi i wọn jẹ.

About ayangalu

x

Check Also

IGP usman

Ọkùnrin tí àwọn adigunjalè yìnbọn mọ́ ní ọjà Bodija ṣì wà láyé — Ọlọ́pàá

Fẹ́mi Akínṣọlá Ìròyìn òkèrè, bí ò lé, a dín.Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti ṣàlàyé bí ìdigunjalè kan tí ìròyìn sọ pé ó gba ẹ̀mí èèyàn kan ṣe wáyé ní ọjà Bódìjà nílùú Ìbàdàn. Agbẹnusọ iléeṣẹ́ ọlọ́pàá, Adéwálé Òṣífẹ̀sọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde tó fi síta lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ọ̀hún pé lọ́jọ́ ẹtì ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣẹlẹ̀. Ó ní arákùnrin kan, Abubakar Ibrahim, ni àwọn adigunjalè kọlù ní nǹkan bíi aago mẹ́ta ku ìṣẹ́jú mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, tí wọ́n sì yìnbọn mọ́ ọ kí wọ́n ...