Home / Àṣà Oòduà / Èmi kò ní àrùn coronavirus – Yahaya Bello

Èmi kò ní àrùn coronavirus – Yahaya Bello

Gomina ipinle Kogi,Ogbeni Yahaya Bollo lo n forere lori ero ayelujara pe ki won se fi orokoro ko oun lorun, oun lo ni arun covid-19 gege bi awon oloselu Kan se n gbee kiri.


O ni loooto ni adari aabo ijoba apapo, Alagba Abba kyari to ni arun naa ba oun lalejo nigba ti o ti orileede Germany de.

O ni o wa ba oun kedun iku mama oun. O ni abewo naa ko muu dandan pe oun gbodo ko arun naa. O ni oun nikan ko ni ko ko arun naa lara re, Alhaji Lai Mohammed naa wa lara awon to fi abewo ye ohun si pelu awon eniyan pataki miiran.


Gomina tun wa ro awon oloselu ti won ko mo ju ki won ko owo je lo,o ni ko dara ki won fi arun coronavirus ko owo je rara. O ni asiko to ye ki iberu Olorun wa ju niyi. O ni oun ko si ni gba ki oloselu kankan lo oun lati ko owo je, eyi lo mu ki oun maa forere pe oun ko ni arun coronavirus rara.

About ayangalu

x

Check Also

ojo keji

Ó San Owó Ilé Ìwé Mi Títí Mo Fi Jáde, Ṣùgbọ́n Mo Fi Májèlé San!

Àti ilé ìwé e gírámà ni èmi àti Kọ́lá ti jọ ń fẹ́ ra wa. Àwọn òbí i mi ò kí ń fẹ́ rí Kọ́lá pẹ̀lú u mi nítorí ààfín ni. Nígbà tí mo fẹ́ wo ile ìwé gíga ni bàbá à mi ní àìsàn an rọ́pá, rọsẹ̀,ọpẹ́lọpẹ́ kọ́lá tó san owó ilé ìwé è mi láti ìgbà tí mo wolé ẹ̀kọ́ gíga títí mo fi jádé. Nígbà ti mo lọ ṣe agùnbánirọ̀ mo pàdé sẹ́nátọ kán,èmi àti ẹ̀ sì ...