Home / Àṣà Oòduà (page 144)

Àṣà Oòduà

Àṣà Oòduà, Asa Ibile Oòduà. Oòduà (Yoruba) je okan ninu awon eya ti o laju ju lode aye yi. Lati igba ti alaye ti daye ni won ti ni eto ati ilana to kun nipa ohun gbogbo ti won nse ni igbesi ayee won.

Foto: Davido se baba gidi fomo re

Sebi tori omo naa la se n sise… Omoomo baba olowo

Read More »

Won ti yan Ooni tuntun ni Ile-Ife

Awon afobaje ilu Ile-Ife ti yan Omooba Adeyeye Enitan Ogunwusi lati idile Giesi gege bi Ooni tuntun bayii. Won si ti fi oruko oba tuntun naa ranse si gomina ipinle Osun, ogbeni Rauf Aregbesola.

Read More »

Mama o fe e gba: Iyabo Ojo ati omo re

Edumare ma pa omo folomo. Ti eniyan ba ri omo Iyabo Ojo, eniyan le sebi boya aburo re ni. Iya gan-an ni ko si fe gba yii. Oga ju!

Read More »

Photos: Meet the New Ooni Of Ife, Oba Adeyeye Enitan Ogunwusi (Kabiyesi O)

ki Ade ko pe lori ki Bata pe lese o,Kabiyesi o.. Adeyeye Enitan Ogunwusi from the Geisi ruling house has been unveiled as the new Ooni of Ife. Moshood Adeoti, secretary to the Osun state government, confirmed this in an ...

Read More »

Madueke ko ti bo ninu ejo, Ile ejo ko fun Saraki nisimi, Abba Moro tun ko sowo EFCC

Madueke o ti bo ninu ejo, Ile ejo o fun Saraki nisimi, Abba Moro tun ko sowo EFCC Olayemi Olatilewa Ile ise ti n risi iwa idaran niluu London, National Crime Agency [NCA] si n ba iwadii won lo ni ...

Read More »

Won ti gbe oye Dokita fun Oba Lamidi Adeyemi III

Leyin ayeye ojo ibi odun metadinlogorin (77) Oba Lamidi Olayiwola Atanda Adeyemi III to waye laipe yii, awon ojongbon tun ti pawopo fi oye Dokita da Alaafin Oyo lola. Ayeye yii lo waye l’Ojoru to koja yii nibi won ti ...

Read More »

Olise dubule aisan leyin ti Emmanuel Emenike dagbere fun egbe Super Eagles

Akoni-moogba egbe agbaboolu Naijiria, Sunday Oliseh ni won ti gbe digbadigba lo si ilu Belgium bayii fun itoju. Ajo ti n dari ere boolu Naijiria, The Nigeria Football Federation lo so eleyii di mimo loju opo won [@thenff] eleyii to ...

Read More »

Ladoja setan lati gba ipo gomina pada lowo Ajimobi ni kootu

Ladoja ati Ajimobi: Taani ipo gomina yoo ja mo lowo ni kootu? Oniroyin: Olayemi Olatilewa Orisun Oniroyin: Twitter Nibayii, won ti kede ojo ti won yoo pari ejo, eleyii ti o je asekagba, to wa laaarin Senato Rasheed Adewolu Ladoja ...

Read More »

Ile ejo ti ran Jimoh lewon leyin to fi ehin ja ori oyan asewo niluu Ibadan

Ile ejo ti ran Jimoh lewon leyin to fi ehin ja ori oyan asewo niluu Ibadan Orisun Oniroyin: Twitter Ile ejo Majisireeti ti n jokoo niluu Ibadan ti ran Ogbeni Sunday Jimoh lewon bayii leyin igba to fi ehin ja ...

Read More »

Won je David Mark, Amaechi ati Fasola lenu bi obi abata

Orisun Oniroyin Twitter Won je David Mark, Amaechi ati Fasola lenu bi obi abata *Didake David Mark n ko awon eniyan lominu *Asa tuntun ti won da: “Mi o gba riba ri laye mi” – Amaechi “Gege bi gomina, mi ...

Read More »